Question 8
Sọ̀rọ̀ lórí ìwúlò Ègè
Observation
Candidates were required to discuss the importance of Ègè Dídá as evident in the excerpt.
Iwúlò Ègè:
(i)      Ègè dídá  kún fún ìjìnlẹ̀ ọ̀rọ̀, ọgbọ́n àti ọ̀rọ̀ apanilẹ́rìn-ín
    (ii)      Ègè  dídá máa ń dá ènìyàn lára yá  
    (iii)     Ó máa ń rán ènìyàn léti ìṣẹ̀lẹ̀  tí ó ti kọ́já tàbí ìtàn tí ó fara sin láti fi kọ́ àwọn èrò  ìwòran lẹ́kọ̀ọ́
    (iv)     Ó máa ń mú orí ẹni wú/yá 
    (v)      Ó jẹ́ ọ̀nà àtijẹ fún àwọn tí ó fi  ń ṣe iṣẹ́ ṣe
    (vi)     Ó  máa ń fọ àwujọ́ mọ́ nípa ṣíṣe àfihàn ìwà ìbàjẹ́/kòtọ́ ní àwùjọ
    (vii)    Ó  máa ń ki ènìyàn nílọ̀ lórí ìwà kòtọ́
    (viii)   Ègè  wà fún ayẹyẹ gbogbo láti mú ìgbádùn bá àwùjọ
    (ix)     Ó wúlò fún ìpolon̄go onírúurú  nǹkan láwùjọ Yorùbá
    (x)      Àwọn Yorùbá máa ń lo Ègè gẹ́gẹ́ bí  orin amúṣẹ́yá.
Only a few candidates attempted this question. Their responses to this question portrayed failure to study the text.